1 Sámúẹ́ lì 17: 33 – 51 Gbogbo eniyn ni o ma n dojukọ awọn omiran kan tabi omiran ninu irin-jo wọn ninu aye. Awọn omiran wọnyi ni a gbọdọ dojukọ, kọju-ija si wọn, ki a si bori wọn bi a ba fẹ ni ilọsiwaju gẹgẹ bi Kristiẹni. Gẹgẹ bi a ti n wo awọn omiran wọnyi lati okeere, ti a si n kawọn gbera gẹgẹ bi ẹni ti o ti ni ijakulẹ kọ ni ọna abayọ, ṣugbọn nini oye nipa ipo rẹ pe̩ lu O̩ lo̩ run ati i isojus̩ e igbe̩ e̩ le re̩ ninu Rè̩ , pè̩ lú ije̩ wo̩ is̩ e̩gun re̩ ni yóò mu o̩ bori. Ifé̩ lati bori awo̩ n omiran aye re̩ ni o da lori igbiyanju re̩ lati ri daju wipe Oruko̩ O̩ lo̩ run ni a i ogo fun ati ife̩ lati rí I wipe liana O̩ lo̩ run fun ye re̩ wa si imus̩ e̩. Onigbagbo̩ gbo̩ do̩ ni oye wipe O̩ lo̩ run ga ju awo̩ n omiran aye wo̩ n lo̩ . Ni Pataki, omiran ti o ga ju dabi e̩ lé̩ te̩ niwaju O̩ lo̩ run alagbara. O̩ na ti a le gba lati bori awo̩ n omiran aye wa ni a ti i han wa lati inu Bíbélı̀. Awo̩ n ohun elo ti o wa laro̩ wo̩ to fun onigbagbo̩ bi igbagbo̩ , adura, iwa-ododo, E̩ ̀jè̩ ati oruko̩ Jésù , ije̩ wo̩ igbagbo̩ ati O̩ ̀ro̩ O̩ ló̩ run ni ti gbe ye̩ wo pe̩ lu aridaju agbara ati ipa wo̩ n lati igba-de-igba., iran-de-iran. Ije̩ wo̩ ti igbagbo̩ wa ma n fi ogo fun O̩ lo̩ run, yoo si tun fun wa ni is̩ e̩gun ti o daju lori gbogbo awo̩ n omiran, ti e̩ mi tabi eyi ti a le fojuri. 1. ÌJÀ ÀTI ÌDOJÚKO̩ LÁTI O̩ WO̩ ́ ÀWO̩ N ÒMÌRÁN Orin Dáfidì 34:19; 1 Sámúé̩ lì 17:1, 10; Ìs̩ e 7:34; 2 Kó̩ ríntì 2:4; 6:4; 8:2; Idojuko̩ awo̩ n omiran, je̩ ko-s̩ eé-máàní fun onigbagbo̩ . Onigbagbo̩ ko̩ o̩ kan ni o ni ipin idojuko̩ lati lati o̩ wo̩ awo̩ n omiran wo̩ nyi, oris̩ iris̩ I awo̩ n omiran ni o si ma n dojuko̩ onikaluku ninu aye. Awo̩ n omiran ti e̩ mi wa, bakan-naa ni awo̩ n omiran ti a le foju ri. Awo̩ n e̩ s̩e̩ iko̩ ko̩ , igbiynju lati gbo̩ nje̩ ge̩ , aisan, ipo̩ nju, aini, idamu, ilo̩ wo̩ o̩ wo̩ , ìdíwó̩ si ilo̩ siwaju, ijakule̩ ni-igba-gbogbo, Aini-aini, ati awo̩ n o̩ po̩ lo̩ po̩ iru awo̩ n nkkan bé̩ è̩ ni o je̩ awo̩ n omiran ti n dojuko̩ o̩ po̩ lo̩ po̩ loni. Awo̩ n omiran miran si leè wa lati mu awo̩ n orile̩ -ede, ijo̩ tabi e̩ bi s̩ ubu. Fun Dafidi, omiran ti n dojuko̩ aye re̩ ni akoko yi je̩ Gòláítì to Gáàtì, e̩ ni ti o fe̩ i oruko̩ O̩ lo̩ run pe̩ gan, ki o si mu ogo-O̩ lo̩ run kuro ni ile̩ náà. Nini imoye ge̩ ge̩ bi onigbagbo̩ is̩ e-pataki lati dojuko̩ awo̩ n omiran-aye wo̩ n, ni yóò fun wno̩ ni anfani is̩ e̩gun ni kiakia láti o̩ wo̩ O̩ lo̩ run. Ete awo̩ n omiran wó̩ nyi ni lati mu o̩ kan, è̩ mí ati wa rè̩ wè̩ sì, kí ó si so̩ wa di alailagbara nipase̩ ibas̩ epo̩ wa pe̩ lu O̩ lo̩ run, nipase̩ mimu igbagbo̩ wa ninu O̩ lo̩ run dinku sí i, ki o si mu wa padanu ilu-o̩ run nike̩ hin. Awo̩ n omiran wo̩ nyi je̩ o̩ ta-o̩ kan re̩ , ti o ko gbo̩ do̩ gba wo̩ n láàyè lati bori. 2. ÌGBE̩ KE̩ ̀LÉ ÀTI ÌJE̩ ́WO̩ ́ ÌGBÀGBO̩ ́ NÍNÚ O̩ LO̩ ́RUN Rómù 8:37; 2 Tímótíù 1:12; Acts 27:22; Fílípì 4:13; 2 Tímòtíù 4:18; 2 Kó̩ ríntì 1:10 “Sáùlù sì wí fú Dáfídì pé, Ìwo̩ kò leè te̩ Fílístínì yí lo̩ láti bá a jà; nitorípé ò̩ dó̩ mo̩ dé ni ìwo̩ …” (1 Sámúé̩ lì 17:33). O je̩ ohun ewu bí ó bba jé̩ wipe igbese̩ wa da lori awo̩ n o̩ ro̩ ti awo̩ n eniyan n so̩ dipo ti o ye̩ ki a gba ohun ti O̩ lo̩ run so̩ nipa awo̩ n omiran ti n dojuko̩ wa. Ninu ikaanu, awo̩ n-abani-damo̩ ran, awo̩ n ara, mo̩ le̩ bi ati awujo̩ , leè gba wa niyan wo̩ nyi, eyi ti yóò já si iparun wa. S̩ ugbo̩ n Dáfìdì wi pe “…Oluwa ti ó gbà mí ló̩ wó̩ kìniún, àti ló̩ wó̩ àmò̩ té̩ kùn, oun náà ni yóò gbà mi ló̩ wó̩ fílístínì yí… Lóni yí ni Olúwa yóò fi ìwo̩ (Gòlíátì) lé mi ló̩ wó̩ , èmi yóò pa ó̩ , èmi yóò si ké orí re̩ kúrù ní ara re̩ …” (1 Sámúé̩ lì 17:37, 46). Igbe̩ ke̩ le ninu O̩ lo̩ run ma n wa nipase̩ ije̩ wo̩ ipò ati ìgbàgbó̩ o̩ wa nínú Rè̩ . Àamı̀ ako̩ ko̩ si ijakule̩ ni ije̩ wo̩ ti o lodi, ibe̩ ru ati ijáàyà, bakan náà gbese̩ ako̩ ko̩ si is̩ e̩gun lori awo̩ n omiran ni ije̩ wo̩ igbagbo̩ ti igbe̩ ke̩ le nínú s̩ is̩ ees̩ e O̩ ló̩ run. Da idi pinu lati wipe ohun ko ni ri Goliati ge̩ ge̩ bi omiran nipase̩ ije̩ wo̩ igbagbo̩ re̩ , oun ko ri is̩ oro náà ge̩ ge̩ bı́i is̩ oro, s̩ ugbo̩ n o pinnu lati O̩ lo̩ run as̩ e̩da Goliati. O je̩ wo̩ is̩ e̩gun, o sì rı́i gba. Awo̩ n o̩ mo̩ -Heberu me̩ te̩ e̩ta je̩ wo̩ is̩ e̩gun wo̩ n lori ina-aileru Nebokadrinesari, wo̩ n sì ríi gba. Obinrin ara-Shunammitı̀ ni je̩ wo̩ wipe “Ó dára” o si ríi gba ba ge̩ ge̩ bi o ti jé̩ wó̩ rè̩ . Márthà je̩ wo̩ iye lori arakunrin-aburo re̩ , Lásárù, o si ríi gba. So̩ ó̩ , kí o sì rí i gba. 3. ÌS̩ E̩Ǵ UN ÀWO̩ N OLÓÒTO̩ ́ NÍPASE̩ ̀ O̩ LO̩ ́RUN E̩ ́ks̩ ódù 14:13; Dáníé̩ lì 11:32; 2 Kó̩ ríntì 2:14; Ìfihàn 12:11; 1 Sámué̩ lì 17:50 Nínú ò ye o̩ mo̩ -eniyan, Da idi je̩ o̩ do̩ mo̩ de, alailagbara, alailoye, s̩ ugbo̩ n lati iwoye ti o̩ run wa, o je̩ jagunjagun alagbara, e̩ ni ti O̩lo̩ run yóò lo lati mu ogo-Rè̩ wa si Israe̩ lì.“Bé̩ è̩ni Dáfídì sí fi kànàkànà òun òkúta s̩ é̩gun Filístínì náà, o si pá a; s̩ ùgbó̩ n idà kò sí ló̩ wó̩ Dáfídi”” (1 Sámúé̩ lì 17:50). Oris̩ iris̩ I is̩ e̩gun ni o ma tè̩ lé ije̩ wo̩ igbagbo̩ . Nigba ti a ba i adura, iwa-ododo, igbagbo̩ ninu o̩ ro̩ O̩ lo̩ run, igboya ijolooto̩ , ati igbo̩ ran, ije̩ wo̩ igbagbo̩ po̩ mo̩ ije̩ wo̩ igbagbo̩ wa ni o ma n mu ki dide lati ran wa lo̩ wo̩ . Is̩ e̩gun lori e̩ s̩ e̩, s̩ isn, ipo̩ nju satani, idojuko̩ , idena, iku, ai-s̩ oriire, ijakule̩ , ati oris̩ iris̩ I awo̩ n omiran miran ni awo̩ n ti o ba gbe O̩ lo̩ run wo̩ n ga nipase̩ ije̩ wo̩